Oluwarotimi Odunayo Akeredolu
Oluwarotimi Odunayo Akeredolu, SAN, or Rotimi Akeredolu, (ọjọ́ ìbí 21 July 1956) jẹ́ olóṣèlú àti agbẹjọ́rò ará Nigeria tó jẹ́ Gómìnà Ìpínlẹ Ondo ní orílẹ̀ edè Nàijíríà lọ́wọ́lọ́wọ̣́. [1] Akeredolu tún jẹ́ ìkan nínú àwọn agbẹjọ́rò àgbà ti ilẹ̀ Nàìjíríà (SAN) tí ó sì jẹ́ ààrẹ ẹgbẹ́ amòfin ti orílẹ̀ edè Nàijíríà ní ọdún 2008.[2]
Ọlọ́lájùlọ Oluwarotimi Odunayo Akeredolu SAN | |
---|---|
![]() Oluwarotimi Akeredolu ní ọdún 2016 | |
Gómìnà Ìpínlẹ Ondo | |
Lọ́wọ́lọ́wọ́ | |
Ó gun orí àga ọjọ́ kẹfàdínlọ́gbọn oṣù kejì ọdún 2017 | |
Asíwájú | Olusegun Mimiko |
Personal details | |
Ọjọ́ìbí |
Oluwarotimi Odunayo Akeredolu 21 Oṣù Keje 1956 Owo, Ìpínlẹ Ondo |
Nationality | Orílẹ̀ edè Nàijíríà |
Ẹgbẹ́ olóṣèlu | All Progressives Congress |
Spouse(s) | Betty Anyanwu-Akeredolu |
Alma mater | Obafemi Awolowo University |
Occupation |
Olóṣèlú agbẹjọ́rò |
Website | aketi.org |
Àwọn ìtọ́kasí
- "Breaking Ondo decides Inec officially declares Rotimi Akeredolu Governor elect". www.premiumtimesng.com. Retrieved 27 November 2016.
- "Nigerian Bar". www.nigerianbar.org. Retrieved 27 November 2016.
This article is issued from
Wikipedia.
The text is licensed under Creative
Commons - Attribution - Sharealike.
Additional terms may apply for the media files.