Oluwarotimi Odunayo Akeredolu

Oluwarotimi Odunayo Akeredolu, SAN, or Rotimi Akeredolu, (ọjọ́ ìbí 21 July 1956) jẹ́ olóṣèlú àti agbẹjọ́rò ará Nigeria tó jẹ́ Gómìnà Ìpínlẹ Ondo ní orílẹ̀ edè Nàijíríà lọ́wọ́lọ́wọ̣́. [1] Akeredolu tún jẹ́ ìkan nínú àwọn agbẹjọ́rò àgbà ti ilẹ̀ Nàìjíríà (SAN) tí ó sì jẹ́ ààrẹ ẹgbẹ́ amòfin ti orílẹ̀ edè Nàijíríà ní ọdún 2008.[2]

Ọlọ́lájùlọ
Oluwarotimi Odunayo Akeredolu
SAN
Oluwarotimi Akeredolu ní ọdún 2016
Gómìnà Ìpínlẹ Ondo
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
ọjọ́ kẹfàdínlọ́gbọn oṣù kejì ọdún 2017
Asíwájú Olusegun Mimiko
Personal details
Ọjọ́ìbí Oluwarotimi Odunayo Akeredolu
21 Oṣù Keje 1956 (1956-07-21)
Owo, Ìpínlẹ Ondo
Nationality Orílẹ̀ edè Nàijíríà
Ẹgbẹ́ olóṣèlu All Progressives Congress
Spouse(s) Betty Anyanwu-Akeredolu
Alma mater Obafemi Awolowo University
Occupation Olóṣèlú
agbẹjọ́rò
Website aketi.org

Àwọn ìtọ́kasí

  1. "Breaking Ondo decides Inec officially declares Rotimi Akeredolu Governor elect". www.premiumtimesng.com. Retrieved 27 November 2016.
  2. "Nigerian Bar". www.nigerianbar.org. Retrieved 27 November 2016.
This article is issued from Wikipedia. The text is licensed under Creative Commons - Attribution - Sharealike. Additional terms may apply for the media files.